1 Kronika 15:2 OYCB

[2] Nígbà náà Dafidi wí pé, kò sí ẹnìkan àyàfi àwọn ọmọ Lefi ni ó lè gbé àpótí ẹ̀rí Ọlọ́run, nítorí OLÚWA yàn wọ́n láti gbé àpótí ẹ̀rí OLÚWA àti láti máa ṣe ìránṣẹ́ níwájú rẹ̀ títí láé.

About this translation

Life Bible app icon
Get the Life Bible app Read offline, sync highlights and notes, and study with your library on any device.