2 Kronika 24:20 OYCB

[20] Nígbà náà, Ẹ̀mí Ọlọ́run wá sórí Sekariah ọmọ Jehoiada wòlíì, ó dúró níwájú àwọn ènìyàn ó sì wí pé, “Èyí ni ohun tí OLÚWA wí: ‘Kí ni ó dé tí ẹ̀yin kò fi tẹ̀lé àṣẹ OLÚWA? Ìwọ kì yóò ṣe rere. Nítorí tí ìwọ ti kọ OLÚWA sílẹ̀, òun pẹ̀lú ti kọ̀ yín sílẹ̀.’ ”

About this translation

Life Bible app icon
Get the Life Bible app Read offline, sync highlights and notes, and study with your library on any device.