2 Kronika 2:6 OYCB

[6] Ṣùgbọ́n ta ni ó le è kọ́ ilé fún OLÚWA, níwọ̀n ìgbà tí àwọn ọ̀run, àní ọ̀run àwọn ọ̀run tó ga jùlọ, kò le è gbà á? Ta ni èmi nígbà náà láti kọ́ ilé fún OLÚWA, bí kò ṣe kìkì àti sun ẹbọ sun ẹbọ níwájú rẹ̀?

About this translation

Life Bible app icon
Get the Life Bible app Read offline, sync highlights and notes, and study with your library on any device.