2 Kronika 36:22 OYCB

[22] Ní ọdún kìn-ín-ní Kirusi ọba Persia, kí ọ̀rọ̀ OLÚWA tí a tẹnu Jeremiah sọ bá à le ṣẹ pé, OLÚWA run ẹ̀mí Kirusi ọba Persia láti ṣe ìkéde ní gbogbo ìjọba rẹ̀, ó sì kọ ọ́ sínú ìwé pẹ̀lú.

About this translation

Life Bible app icon
Get the Life Bible app Read offline, sync highlights and notes, and study with your library on any device.