2 Kronika 5:7 OYCB

[7] Nígbà náà ni àwọn àlùfáà gbé àpótí ẹ̀rí ti májẹ̀mú OLÚWA wá sí ipò rẹ̀, sí ibi inú lọ́hùn ún ilé OLÚWA, Ibi Mímọ́ Jùlọ, wọ́n gbé e sí abẹ́ ìyẹ́ àwọn kérúbù.

About this translation

Life Bible app icon
Get the Life Bible app Read offline, sync highlights and notes, and study with your library on any device.